Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 13:21:45
Ìgbìmọ̀ tó ń rí sí ìwà ọmọlúàbí ní ilé aṣòfin àgbà da ẹjọ́ ti Natasha pè tako Akpabio nù lọ́jọ́rú, wọ́n ní ẹ̀sùn rẹ̀ kò lẹ́sẹ̀ nílẹ̀.
Àìsàn ẹ̀jẹ̀ rúru ló kọ́ ṣe 'I Sho Pepper'', ó ń pọ̀ ẹ̀jẹ̀ lórí ahọ́n, dákú fọ́jọ́ mẹ́sàn -án, kí ọlọ́jọ́ tó dé - Yetunde Ogunsola
Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 08:58:55
Ọdun 1972 ni Yetunde Ogunsola to jẹ ọmọbibi ilu Ilesha bẹrẹ ere tita lẹyin to darapọ mọ ẹgbẹ oṣere oloogbe ''I Sho Pepper.''
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 11 Oṣù Ìgbé 2023 ní 06:13:59
Lásìkò àwẹ̀, àwọn ènìyàn máa ń séra fún oúnjẹ jíjẹ, omi mímu àti bẹ́ẹ̀ bẹ́ẹ̀ lọ àmọ́ ẹ wo àwọn àrùn tó le ti ìdí ààwẹ̀ súyọ.
Ọ̀gá tẹ́lẹ̀ fún iléeṣẹ́ arìnrìnàjò tí ayé ń kígbe pé Boko Haram pa, ilé ìtura ló kú sí l'Abuja - Ọlọ́pàá
Ọjọ́bọ, 6 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 05:48:09
Atẹjade ti Alukoro ọlọpaa fun ilu Abuja, Josephine Adeh, buwọ lu, tẹsiwaju pe ko pẹ ti Parradang wọ yara rẹ ni alejo obinrin kan wa a ki i.
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 16:46:06
Ẹkùn Sahel ní Afirika ní ìdá mọ́kànléláàádọ́ta (51%) nínú ìdá ọgọ́rùn-ún ikú látara ìgbéṣùmọ̀mí ti wáyé lọ́dún 2024.
Ìgbésẹ̀ láti káwọn ọmọ Nàìjíríà tí kò ní ìwé ìgbélùú l'Amẹrika padà wálé, ti bẹ̀rẹ̀ tipẹ́ - Mínísítà
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:19:39
Ọgbẹni Tuggar sọ pe igbesẹ kiko awọn ọmọ Naijiria ti ko niwe igbelu ti bẹrẹ ṣaaju ki Aarẹ Donald Trump to wọle ibo aarẹ Amẹrika fun saa keji.
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 11:26:46
BBC dara pọ mọ awọn osisẹ ileesẹ to n satunse kebu itakun agbaye to wa labẹ okun Ghana lati mọ bi wọn ti n se atunse awọn kebu inu okun naa.
Ìdí rèé tí Jandor ṣe fi PDP sílẹ̀ àti ohun tó mú kó kùnà láti dojú Sanwo-Olu bolẹ̀ lásìkò ìbò gómìnà l‘Eko
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:00:40
Jandor sọrọ yii lori eto ileeṣẹ tẹlifisan kan lalẹ ọjọ Iṣẹgun amọ o ti kede saaju pe oun ti fi ẹgbẹ oselu PDP silẹ.
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 08:19:59
Aarẹ Volodymyr Zelensky loun kabamọọ ihuwasi oun lasiko itakurọsọ to waye laarin oun ati Donald Trump nileeṣẹ ijọba Amẹrika.
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 08:13:55
Atẹjade ti Kọmiṣanna fun eto iroyin ati ilaniloye nipinlẹ Oyo, Dotun Oyelade, fi sita lo fidi eyi mulẹ.
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 06:30:37
Èyí ló ń jẹyọ nínú àbọ̀ kan tí àjọ The Lancet ṣẹ̀ṣẹ̀ gbé jáde lórí ìwádìí tí wọ́n ṣe ní àwọn orílẹ̀ èdè tó lé ní igba.
Ọjọ́rú, 5 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 06:09:53
Ajọ Iṣọkan Agbaye, UN, lati ọdọ ẹka rẹ to n ri si ọrọ ọmọde; UNICEF, ni àwọn agbébọn ń fipá bá àwọn ọmọ ọdún kan lo pọ ni Sudan.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 11:22:17
Ọpọ awọn alagbata epo lo sọ pe ileeṣẹ NNPCL ko tii sọ fawọn pe adinku ti ba iye tawọn yoo maa ta epo fawọn bayii.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 17:08:41
Nǹkan bíi aago kan ọ̀sán ni ìjàm̀bá náà wáyé nígbà tí ọkọ̀ Mazda kan tó ní nọ́mbà KJA949YJ ṣàdédé gbiná.
Ọjọ́ Ajé, 15 Oṣù Ìgbé 2024 ní 11:20:59
Má jẹ́ kí etí rẹ ó di sí gbogbo ìròyìn ohun tó ń lọ ní Naijiria àti káàkiri àgbáyé. Mọ̀ nípa wọn lórí ìkànnì Whatsapp rẹ
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:45:36
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa ipinlẹ Imo, DSP Okoye Henry, lo fidi ọrọ yii mulẹ ninu atẹjade kan to fi sita.
Èmi àti ẹ̀gbọ́n mi, Ayodele Fayose ń yan odì ọ̀lọ́jọ́ pípẹ́, bí a kò bá sọ̀rọ̀ láyé, á pàdé lọ́run - Isaac Fayose
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 09:39:35
BBC Yorùbá bá Isaac, tíí ṣe àbúrò gómìnà tẹ́lẹ̀ ní ìpínlẹ̀ Ekiti, Ayodele Fayose sọ̀rọ̀, ó ṣàlàyé àjọṣepọ̀ pẹ̀lú ẹ̀gbọ́n rẹ̀, ìdí tó ṣe ní aya àti ọmọ púpọ̀ pẹ̀lú ètò ìṣèlú.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:20:48
Onimọ ni awọn nnkan miran wa tawọn eeyan ro pe o le ba aawẹ jẹ, ṣugbọn to jẹ wọn ko ṣe akoba kankan fun aawẹ.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:15:56
A ba awọn obinrin mẹta sọrọ lorilẹede Kenya, wọn si fidi ẹ mulẹ fun wa pe awọn ti bẹrẹ si i fi ihoho awọn han loju opo naa nigba ti ọjọ ori awọn ṣi wa laaarin mẹẹẹdogun si mọkandinlogun.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 07:15:19
Kọmiṣọnna fun aṣa ati irinajo igbafẹ nipinlẹ Oyo, Wasiu Olatubosun ti fidi rẹ mulẹ pe iroyin ofege ni iroyin naa, o ni koko lara Olubadan le bi ọta.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 10:51:24
Ninu atẹjade kan ti wọn fi sita lọjọ Aiku ọsẹ yii ni Aarẹ CAN, Arcbishop Daniel Okoh ti ṣapejuwe igbesẹ naa bii iwa aitọ si awọn akẹkọọ ti ki i ṣe Musulumi.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:29:51
Olabiyisi ẹni ọdun mọkandinlọgbọn lawọn ẹṣọ Amotekun doola lakata awọn ajinigbe lẹyin wakati mẹẹdogun ti wọn ti jigbe.
Mo jẹ́rìí aya mi lórí ẹ̀sùn tó fi kan Akpabio, mo ti rọ̀ ọ́ tẹ́lẹ̀ pé kó fi aya mi lọ́rún silẹ̀ - ọkọ Natasha
Ọjọ́ Àìkú, 2 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 16:04:06
Atẹjade ti Uduaghan fi sita ni oun ko fẹ da si ọrọ naa tẹlẹ ṣugbọn awọn nnkan to n jade lori rẹ, lo jẹ ki oun tẹnu bọ ọrọ.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 06:45:09
Ninu atẹjade kan to fi sita lẹyin ipade igbimọ alaṣẹ NLC niluu Yola ni ipinlẹ Adamawa lopin ọsẹ to kọja ni ẹgbẹ naa ti ṣapujewe erongba ijọba lati ṣe afikun owo ina mọnamọna gẹgẹ bi igbesẹ ti ko dara fawọn oṣiṣẹ ati fun gbogbo araalu.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 08:05:26
Agbẹnusọ ileeṣẹ ọlọpaa, Ahmed Wakil, sọ pe lalẹ ọjọ Abamẹta opin ọsẹ to kọja ni iṣẹlẹ yii waye lagbegbe Fadamam Mada ni Bauchi.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 07:08:21
Lọdun 2024, eeyan mọkanla ni ikọ Hisbah mu lórí ẹsun pe wọn n jẹun ọsan nilu Kano.
Ọjọ́ Àìkú, 2 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 17:15:44
Muhibi ṣalaye iru idẹyẹsi to foju ri latọdọ awọn alabaṣiṣẹ rẹ gẹgẹ bi awakọ.
Wọ́n gbé gbogbo àwọn obínrin lọ - Àwọn obìnrin tí wọ́n fipá bá lò pọ̀ lọ́gbà ẹ̀wòn DR Congo sọ ìrírí wọn
Ọjọ́ Àìkú, 2 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:40:15
Oun ni ọkunrin keji ti yoo fipa balopọ ninu ọgba ẹwọn Munzenze ree. O daku lasiko ti akọkọ waye.
Ọjọ́ Ìsẹ́gun, 4 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 06:41:25
Agbẹnusọ fun ileesẹ ọlọpaa nipinlẹ Bauchi ni lọjọ keji aawẹ Ramadan ni awọn ero to pọ naa ti bẹrẹ si ti ara wọn, nibẹ si ni eeyan mẹrin ti kọkọ dagbere faye.
Ọjọ́ Ajé, 3 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 17:45:05
Ọnarebu Noheem Adams to n ṣoju ẹkùn Eti-Osa lo fa Obasa kalẹ pe ki wọn dibo fun un, Ọnarebu Nureni Akinsanya lati Mushin si ṣe ikeji aba naa.
Ọjọ́ Àìkú, 2 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 11:49:48
Femi Falana sọ pe Ibrahim Babangida fagile eto lati da ijọba pada fun alagbada ni igba mẹrin ọtọtọ pẹlu agbekalẹ ofin ologun nọmba 25 to ṣe lọdun 1987.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 15:19:13
Ninu atẹjade kan ti alaga Ajọ NAFDAC, Ọjọgbọn Mojisola Adeyeye ni NAFDAC ko fi igbakankn se akọsilẹ fun oogun Tafrodol tabi Royal 225 tabi Tramadol gan .
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 06:37:01
Iwọn gilaasi ti wọn ri ni ọpọlọ rẹ jẹ iwọn sẹntimita kan si meji, ti awọn kan si jẹ iwọn milimita.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 17:58:48
Ikede yii lo jade loju opo ayelujara agbẹnusọ fun ileeṣẹ ọlọpaa, Olumuyiwa Adejobi lọjọ Ṣatide.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 09:00:15
Ileesẹ panapana ipinlẹ Kwara ṣalaye ninu atẹjade kan ti agbẹnusọ Ileesẹ naa, Hassan Hakeem Adekunle, fi lede pe iwadii awọn fi han pe tirela to ko ajilẹ naa lo fẹ ya tanka epo ọhun lati ẹyin sugbọn ti o kọ lu u lẹgbẹ.
Ọjọ́ Àìkú, 2 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 09:05:42
Oloye James Olawale salaye pe gbogbo nkan ti wọn fi n bọ oriṣa Ogun naa ni wọn fi n bọ Apata Ansoogun bii aja, epo, ẹmu, obi ati bẹẹ bẹẹ lọ.
Ọjọ́ Ajé, 24 Oṣù Èrèlè 2025 ní 13:43:55
Ni bayii, ẹ le ri iroyin yajoyajo, iroyin lori nnkan to n lọ atawọn iroyin lori iṣẹlẹ lawujọ ti BBC Yoruba ṣe akojọpọ rẹ lori foonu yin.
Ọjọ́ Àbámẹ́ta, 1 Oṣù Ẹrẹ̀nà 2025 ní 12:45:36
Aarẹ Bola Tinubu ni ''awẹ Ramadan ọdun yii ṣe pataki tori o bọ si asiko ti eto ilọsiwaju ati ireti tuntun n lọ lọwọ ni Naijiria.''